Noimot Salako-Oyedele
From Wikipedia, the free encyclopedia
Nòímòt Sàlàkó -Oyèdélé, jẹ́ onímọ̀ ẹ̀rọ, olósèlú, onímọ̀ nípa ohun ìní, omo bíbí orílẹ̀ èdè Nàíjírìa ti a bí ní ọdún 1967,bàbá rẹ̀ Lateef A. Salako NNOM, CON jẹ́ Ọ̀jọ̀gbọ́n onímọ̀ ìjìnlẹ̀ nípa ẹ̀kọ́ àwọn òògùn àti Olùkọ́ ni fásitì ilẹ̀ Ìbàdàn. Ó jẹ́ igbákejì gómìnà ìpínlẹ̀ Ògùn, orílẹ̀ èdè Nàijiria. Ó di igbákejì Gómìnà ìpínlẹ̀ Ògùn lẹ́hìn tí ó borí pẹ̀lú Dàpọ̀ Abíọdún, Gómìnà ìpínlẹ̀ Ògùn, ní ọdún 2019 nínú ìdìbò gómìnà fún ìpínlẹ̀ Ògùn, lábẹ́ àsìá All Progressive Congress (APC) sáájú Yétúndé Ọnànúgà, igbákejì Gómìnà ìpínlẹ̀ náà tẹ́lẹ̀.
Quick Facts Igbá kejì Gómìnà ìpìnlẹ̀ Ògùn, Asíwájú ...
Noimot Salako-Oyedele | |
---|---|
Igbá kejì Gómìnà ìpìnlẹ̀ Ògùn | |
Lọ́wọ́lọ́wọ́ | |
Ó gun orí àga 29 May 2019 | |
Asíwájú | Yetunde Onanuga |
Àwọn àlàyé onítòhún | |
Ọjọ́ìbí | {{ Ọjọ Ìbí àti ọjọ orí, Ọjọ kẹjọ, osù kínní {Seere}, Ọdún 1966.}} Nigeria |
Ẹgbẹ́ olóṣèlú | All Progressives Congress |
(Àwọn) olólùfẹ́ | Alhaji Bode Oyedele |
Profession | Real Estate Consultant |
Close