Ameyo Adadevoh

Oníṣègùn From Wikipedia, the free encyclopedia

Ameyo Adadevoh
Remove ads

Ameyo Stella Adadevoh (tí a bí ní ọjọ́ Kẹtàdínlọ́gbọ̀n oṣù Kẹ̀wá ọdún 1956 tí ó sì fi ayé sílè ní ọjọ́ kàndínlọ́gún oṣù kẹjọ ọdún 2014) jẹ́ onímọ̀ ìṣẹ́gun òyìnbó ọmọ orílẹ̀-èdè Nàìjíríà.

Quick facts Ìbí, Aláìsí ...
Thumb
Ojú ọnà kan tí wọ́n sọ lórúkọ tẹ́lé Ameyo Adadevoh

Àwọn ènìyàn ma ń ròyìn rẹ̀ fún ipa tí ó kó nínú mímú owó ààrùn Ebola Virus balẹ̀ ní Nàìjíríà nípa mímú ẹni àkọ́kọ́ tí ó kọ́kọ́ ní ààrùn náà, Patrick Sawyer, sí ibi ìpamọ́ bí ó tilè jẹ́ wípé àwọn ìjọba Làìbéríà tako fí fi Patrick sí ìpamọ́.[1][2][3] Ní ọjọ́ kẹrin oṣù kẹjọ ọdún 2014, ìwádìí àyẹ̀wò fihan pé ààrùn Ebola wà lára rẹ̀, àwọn onímọ̀ ìṣẹ́gun sì bẹ̀rẹ̀ ìtójú fún lé sẹ̀kẹ́sẹ̀.[4] Ṣùgbọ́n Adadevoh fi ayé sílè ní ọ̀sán ọjọ́ kan dínlógún oṣù kẹjọ ọdún 2014.[5][1] Ó fi ọkọ rẹ̀, Afolabi àti ọmọ rẹ̀, Bankole sílè sáyé.

Remove ads

Àwọn Ìtọ́kasí

Loading related searches...

Wikiwand - on

Seamless Wikipedia browsing. On steroids.

Remove ads