Fẹ́mi Adébáyọ̀
Òṣéré orí ìtàgé From Wikipedia, the free encyclopedia
Remove ads
Fẹ́mi Adébáyọ̀ (tí wọ́n bí ní Ọjọ́ kọkànlélọ̀gbọ̀n oṣù Kejìlá ọdún 1973) [1] jẹ́ amòfin, gbajúmọ̀ òṣèré, olóòtú àti olùdarí sinimá àgbéléwò ọmọ bíbí Ìlọrin ni ìpínlẹ̀ Kwara. Bákan náà Fẹ́mi Adébáyọ̀, títí di ọjọ́ kọkàndínlọ́gbọ̀n oṣù karùn-ún ọdún 2019 jẹ́ Olùdámọ̀ràn Pàtàki lórí àṣà, ìrìn-afẹ́ àti iṣẹ́-ọ̀nà fún Gómìnà ìpínlẹ̀ Kwara àná, Abdulfatah Ahmed. Ó jẹ́ ọ̀kan lára àwọn ọmọ gbajúgbajà òṣèré sinimá àgbéléwò, Adébáyọ̀ Sàlámì, tí gbogbo ènìyàn mọ̀ sí Ọ̀gá Bello.
Remove ads
Ìbẹ̀rẹ̀pẹ̀pẹ̀ ayé àti ètò ẹ̀kọ́ rẹ̀
Wọ́n bí Adebayo ní ọjọ́ kọkànlélọ́gbọ̀n oṣù Kejìlá (Ọ̀pẹ) ọdún 1978 ní ìpínlẹ̀ Èkó, ní orílẹ̀-èdè Nàìjíríà. Bàbá rẹ̀, Adebayo Salami (Oga Bello) náà jẹ́ òṣèré tíátà àti agbéréjáde,[2] tó jẹ́ ọmọ bíbí ìlú Ilorin ní Ìpínlẹ̀ Kwara.[3]
Àwọn Ìtọ́kasí
Wikiwand - on
Seamless Wikipedia browsing. On steroids.
Remove ads