Jemima Osunde
Òṣéré orí ìtàgé From Wikipedia, the free encyclopedia
Remove ads
Jemima Osunde tí wọ́n bí ní ọgbọ̀njọ́ oṣù Kẹrin ọdún 1996. [1] jẹ́ òṣèré orí-ìtàgé , model àti olóòtú ètò lórí ẹ̀rọ amóhù-máwòrán Ọmo orílẹ̀-èdè Nàìjíríà.[2] Ó di ìlú-mòọ́ká lẹ́yìn tí í ó kópa gẹ́gẹ́ bí ẹ̀dá-ìtàn "Jemima" nínú eré àtìgbà-dégbà onípele ti Shuga.[3]Wọ́n yan Osunde fún amì-ẹ̀yẹ ti Best Actress in a Leading Role àyẹyẹ 15th Africa Movie Academy Awards ẹlẹ́kẹẹ̀ẹ́dógún irú rẹ̀ tí yóò wáyé fún ipa rẹ̀ tí ó kó nínú eré The Delivery Boy (2018).[4]
Remove ads
Ìbẹ̀rẹ̀ ayé rẹ̀
Wọ́n bí Osunde sí ìlú Edo, ó kẹ́kọ̀ọ́ nípa physiotherapy ní ilé-ẹ̀kọ́ Yunifásitì Ìpínlẹ̀ Èkó.[5][6][7]Ó kópa nínú eré Jungle Jewel lẹ́yìn tí àbúrò bàbá rẹ̀ gbàá níyànjú láti máa lọ ṣeré ìtàgé.
Ó kópa bí ẹ̀dá-ìtàn "Laila" nínú eré àtìgbà-dégbà onípele ti MTV Shuga.Ó pa ìkópa tì nínú eré yí nígbà tí wọ́n gbé eré náà lọ sí orílẹ̀-èdè South Africa, àmọ́ ó tún bá wọn kópa padà nígba tí eré náà padà sí orílẹ̀-èdè Nàìjíríà. [8] Ní ọdún 2018, ó kópa nínú eré Rumour Has it pẹ̀lú òṣèré mìíràn bíi: Linda Ejiofor lórí NdaniTV's .[9][10]
Osunde tún báwọn kópa nínú ìpele keje lórí MTV Shuga lásìkò ìsémólé COVID-9 .[11][12].
Remove ads
Ètò-ẹ̀kọ́ rẹ̀
Ní ọdún 2019, Osund jáde ẹ̀kọ́ nílé ẹ̀kọ́ Yunifásitì Èkó nínú ìmọ̀ physiotherapy.[13]
Àwọn àṣàyàn eré rẹ̀

Àwọn eré amóhù-máwòrán
- Shuga
- This Is It (2016–2017)
- Rumour Has It (2018)
Àwọn ìtọ́kasí
Àwọn Ìtàkùn ìjásóde
Wikiwand - on
Seamless Wikipedia browsing. On steroids.
Remove ads